Adelaja ni, owo ti awọn pasitọ naa n gba bii owo irugbin ‘Seed’, ko ba ofin Ọlọrun mu, owo ọrẹ nikan ni Ọlọrun fi ọwọ si.
O fikun pe, atinuda gan ni idamẹwa jẹ, tori ofin majẹmu laelae ni, ko si ninu majẹmu tuntun, ti Jesu ati awọn ọmọ ẹyin rẹ ko si gba idamẹwa ri nigba aye wọn.
Oludasilẹ ijọ Embassy of God naa tun ni, ẹni to ba wu lee da idamẹwa, ida kan, meji abi ida ọgbọn, lai jẹ pe ẹnikẹni sọ iye ti yoo da fun Ọlọrun.
Full clip of my attempts to communicate in Yoruba language